Jump to content

Òṣogbo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Oba Jimoh Olanipekun Oyetunji, Laroye II Ataoja Oshogbo-min


Òṣogbo (2015)
Location of Osogbo in Nigeria
Ìtàn ṣókí nípa Ìlú Òṣogbo láti ẹnu ọmọ bíbí Òṣogbo

Òṣogbo jẹ́ ìlú ńlá kan ní ìpílẹ̀ Ọ̀ṣun ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, bákan náà ni ó jẹ́ olú ìlú fún ìpínlẹ̀ náà ní apá ìwọ̀ Oòrùn ilẹ̀ Nàìjíríà. Ọ̀gbẹ́ni Adémó̩lá Adélékè ni Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun lọ́wọ́lọ́wọ́. Òṣogbo di olú ìlú fụ́n Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ní ọdun 1991.[1] Bákan náà ni ó tún jẹ́ olú ilé-iṣẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ fún ìlú Òṣogbo, tí ilé-iṣẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ náà sì wà ní Òke Báálẹ̀, nígbà tí ìjọba ìbílẹ̀ Ọlọ́rundá ń ṣojú agbègbè Ìgbóǹnà nílú Òṣogbo.[1][2]

Àwọn ìtọ́ka sí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àdàkọ:Oluilu ipinle Nàìjíríà

  1. 1.0 1.1 Jiboye, Adesoji David (1 March 2014). "Significance of house-type as a determinant of residential quality in Osogbo, Southwest Nigeria" (in en). Frontiers of Architectural Research 3 (1): 20–27. doi:10.1016/j.foar.2013.11.006. ISSN 2095-2635. http://www.sciencedirect.com/science/article/pii/S2095263513000812. 
  2. "Supreme Court affirms Gboyega Oyetola's election as Osun Governor". Premium Times Nigeria. 2019-07-05. Retrieved 2019-09-18. 
pFad - Phonifier reborn

Pfad - The Proxy pFad of © 2024 Garber Painting. All rights reserved.

Note: This service is not intended for secure transactions such as banking, social media, email, or purchasing. Use at your own risk. We assume no liability whatsoever for broken pages.


Alternative Proxies:

Alternative Proxy

pFad Proxy

pFad v3 Proxy

pFad v4 Proxy